Jeremiah 31:37
37
Èyí ni ohun tí
Olúwa
wí:
“Àyàfi tí a bá lé àwọn ọ̀run lókè
tí ìpìlẹ̀ ayé sì di àwárí ní ìsàlẹ̀,
ni èmi yóò kọ àwọn Israẹli
nítorí ohun gbogbo tí wọ́n ti ṣe,”
ni
Olúwa
wí.
Copyright information for
YorBMYO